Home / Art / Àṣà Oòduà / Òdóbìnrin orílè-èdè Nàíjíríà kan se ayeye ojó ìbí rè tí ó sì há oúnje fún àwon aláìní.

Òdóbìnrin orílè-èdè Nàíjíríà kan se ayeye ojó ìbí rè tí ó sì há oúnje fún àwon aláìní.

    Òdómobìnrin orílè-èdè Nàíjíríà ni ó pinnu láti se ayeye ojó ìbí ní àrà òtò, nígbà tí a ri tí ó n pín oúnje àti àwon nkan míràn fún àwon aláìní, omodé àti àwon èèyàn míràn . ònà ni a ti pàdé rè ní Owerri ní ìjoba ìpínlè Imo .

Òpòlopò àwon èèyàn ni ó yìn….

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...