Home / Art / Àṣà Oòduà / Ogún ènìyàn jàjà bọ́ lọ́wọ́ coronavirus
contain corona virus

Ogún ènìyàn jàjà bọ́ lọ́wọ́ coronavirus

Ogún ènìyàn jàjà bọ́ lọ́wọ́ coronavirus
Ìròyìn láti ọwọ́ Yínká Àlàbí


Ni ipinle Eko ni ori ti ko ogun eniyan yo ni ile iwosan ti won ti n toju awon ti kokoro Covid-19 n ba ja.


Bi o tile je pe won ni ko si oogun kan gbogi fun aisan naa sugbon Eledua n fun ipinle Eko se lati ni aseyori lori itoju awon alaisan naa. Ti a ko ba gbagbe, arakunrin omo orileede Italy ni o koko gba iwosan naa ki awon meta miiran, marun-un miiran ki mokanla to kun-un ni oni ojo keji, osu kerin odun ti a wa yii.


Ijoba apapo, ipinle ati ibile pelu ajo NCDC ni ki awon eniyan ma se dawo imototo duro ki onikaluku si gbe ile re fun igba die ki arun buruku naa le kase nile patapata.

About ayangalu

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...