Home / Art / Àṣà Oòduà / Olùsó àgùntàn David Ibiyeomie gba okò bògìnì fún èbùn ojó ìbí rè nígbà tí ó pé odún márùnléláàdóta .

Olùsó àgùntàn David Ibiyeomie gba okò bògìnì fún èbùn ojó ìbí rè nígbà tí ó pé odún márùnléláàdóta .

     Gégé bí Innocent se so, olùsò àgùntàn rè pastor David Ibiyeomie ni won fún ní okò bògìnì tí ó wà ní ìsàlè yí gégé bi èbùn ojó ìbí rè, sé kò dùn gbó l’étí ni?.

Ó ye kí á rántí wípé gbajúgbajà olùsó àgùntàn tí o fi Port Harcourt se ibùgbé se ayeye ojó ìbí rè ní ojó díè séyìn…

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...