Home / Search Results for: Ogun state (page 37)

Search Results for: Ogun state

Adebayo Faleti

Yoruba hero and Actor Adebayo Faleti passes on !

Ẹyẹ o dédé bà’lorule ó, ọ̀rọ̀ leye ń gbó o. (Saworoide). Adebayo Faleti has gone to lay with the ancestors. He will be missed greatly.   Sun re O ! Ase   The arts community mourns the passage of multitalented ...

Read More »
policeman

Ìbon ba àwon ajínigbé nígbà tí won ń dúnà pàsípààrò lówó ní ìjoba ìpínlè Abia. 

Àwon ajínigbé mérin, èyí tí won ti ń da ìpínlè Abia àti agbègbè rè láàmú. Won ti ń gbìyànjú àti parun tí àwon òtelèmúyé so mó Omoba Division ní ojó ketàdínlógún osù keje (19th July ,2017) ní Ovungwu, Isiala -Ngwa ...

Read More »
Odua Group

Lagos To Join Odu’a Group Of Companies

Lagos State will formally join Odu’a Group of Companies as its sixth owner-state in the next three months, The Nation has learnt. The Group Managing Director (GMD) of the regional investments conglomerate, Mr Adewale Raji, announced this in Ibadan, Oyo ...

Read More »

Lagos Deposes Baale Who Faked Own Kidnap

By Ndubuisi Michaels The Lagos State Government on Sunday deposed the suspended Baale of Shangisha in Magodo, Chief Yusuf Ogundare for faking his abduction which allegedly took place on July 5 along the Center for Management Development (CMD) Road in ...

Read More »
oyo

Aseyin Charges People Of Ipapo And Oke Amu To Foster Peace In Their Boundaries

People of Itesiwaju local government area of Oyo State have been urged to complement efforts of Senator Abiola Ajimobi led government by ensuring peaceful co-existence with people of Iseyin Land that share boundaries with them. The Chairman, Conference of Obas ...

Read More »
Olubadan

Olúbàdàn kìlò kí won má se jàgídíjàgan bí odún egúngún se fé bèrè.

Gégé bí odún egúngún odoodún se ma bèrè l’óla, ojó ajé, ní ìlú Ibadan, ní ìpínlè Oyo, Olúbàdàn ti ilè Ibadan, oba Saliu Akanmu Adetunji ti pè fún àláfíà láti òdò àwon eléégún àti àwon tí ó ń tèle tí ...

Read More »
kai

Ìjoba ìpínlè Èkó dá àwon òsìsé KAI dúró tí won sì fi LAGESC r’ópò won.

Ìjoba ìpínlè Èkó, lábé àse Gómìnà, láti jé kí ìlosíwájú bá ètò ìlera ti dá àwon òsìsé KAI (kick against indiscipline) dúró tí won sì fi LAGESC r’ópò won. Ìgbésè náà, gégé bí ìjoba ìpínlè náà, jé òkan lára ìsàkóso ...

Read More »
evans

Àyàngbàjù! Ògbó-n-tarìgì gbómogbómo, Evans pe ògá olóòpá l’éjó,

**Àti Àwon Méta Míràn Látàrí Àtìmólé Rè Ní Gbogbo Ìgbà. Ògbó-n-tarìgì gbómogbómo, Chukwudumeme Onuwuamadike tí ìnagije rè ńjé Evans, ó ti pe ògá olóòpá l’éjó, tí orúko rè ńjé Ibrahim Idris àti àwon méta míràn ní ilé ejó gíga ti ...

Read More »
transifoma

Gómìnà Yahaya Bello ri èro amúnáwà (Transformer) gégé bí isé rè àkókò ní ìpínlè Kogi. 

Gégé bí ìròyìn se so, Gómìnà ìpínlè Kogi: Yahaya Bello ri èro amúnáwà tí agbára rè tó Egbèédógún (300KVA) ní òpópónà kan ní Lokoja gégé bí isé rè àkókó léyìn tí ó ti lo odún kan àti ààbò lórí ipò. ...

Read More »
pasito

Owó te olùsó àgùntàn(pastor) èké kan nígbà tí ó ń gbìyànjú láti ri ohun tí a kò mò sí ilé onílé. 

Olùsó àgùntàn èké kan tí a mò sí Osinachi Christopher láti ìpínlè Abia ni won fi s’èsín léyìn ìgbà tí owó ti tèé nígbà tí ó ń gbìyànjú à ti ri ohun tí a kò mò sí ilé onílé ní ...

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb