Home / Tag Archives: Àṣà Yorùbá (page 35)

Tag Archives: Àṣà Yorùbá

Igbo pàdé calabar, àwòrán kí won tó se ìgbéyàwó bí okùnrin náà se fi owó kó ìdí arábìnrin náà.

Àwòrán èyí kí ó tó di ojó ìgbéyàwó ti arákùnrin Igbo tí a mò sí Ofor, tí ó ti se tán láti fé aya àfésónà rè Witney tí ó jé Calabar ní ojó etì, ojó kejìdínlógún osù kokànlá odún yí ...

Read More »

Omoba Eze Madumere àti Chioma Rosemary kí omobìnrin kú àbò.

    Igbékejì Gómìnà ìpínlè Imo , Omoba Eze Madumere àti aya tí ó sèsè fé, Omoba Chioma Rosemary Madumere kí omobìnrin káàbò léyìn osù méjì léyìn ìgbéyàwó, won ti bí omobìnrin. Igbékejì Gómìnà ni ó pín àwòrán yí tí ...

Read More »

Peter Okoye àti Lola Omotayo se ayeye odú kerin ìgbéyàwó won.

   Olórin , Peter Okoye ti Psquare àti ìyàwó rè , Lola Okoye tí won ti wà papò fún bí odún métàlá se ayeye odún kerin ìgbéyàwó won.

Read More »

A ya àwòrán Bola Tinubu àti Osinbajo.

   Igbékejì Ààre Osinbajo àti baba ìsàlè egbé APC Bola Tinubu ya àwòrán papò lánàá níbi fífi ìwé l’ólè tí okàn lára àwon agbenuso ilé ìgbìmò so lórí bí Ààre Buhari se n gbógun ti ìwà jegúdújerá.

Read More »

Toke Makinwa ti ko àkosílè èróngbà rè fún odún 2018.

    Toke Makinwa ti ko èróngba rè fún odún 2018,tí ó sì ti setán láti gba odún náà towótosè . Lára àwon èróngbà rè ni Olórun, Ebí abbl.

Read More »

Patience Jonathan níbi ayeye ìgbéyàwó omobìnrin asojú ilé ìgbìmò asòfin, Sekibo.

     Aya Ààre télè, Dame Patience Jonathan yo ní àrà òtò láti yé adojú ilé ìgbìmò asòfin Thompson Sekibo bí ó se no àkóbí rè lówó níbi ìgbéyàwó yí ní ìlú Ogun.

Read More »

A ya àwòrán Bola Tinubu àti Osinbajo.

   Igbékejì Ààre Osinbajo àti baba ìsàlè egbé APC Bola Tinubu ya àwòrán papò lánàá níbi fífi ìwé l’ólè tí okàn lára àwon agbenuso ilé ìgbìmò so lórí bí Ààre Buhari se n gbógun ti ìwà jegúdújerá.

Read More »

Òdóbìnrin àtúnbí yí ti sí tàtúù apá rè pèlú irin gbígbóná.

    Òdóbìnrin àtúnbí tí ó jé omo orílè èdè Nàíjíríà, ti jó owó rè pèlú irin gbígbóná ní èróngbà láti pa tàtúù owó rè, gégé bí ó se so wípé èsè ni , ó sì le dínà láti wo ...

Read More »

Àwòrán tí ó yanilénu tí Empress.

Njamah òsèré Nàíjíríà, Empress Njamah tí ó kò láti ní adé orí , látàrí wípé ó ní owó lówó gbe lo sí orí èro ayélujára láti pín àwòrán tí ó rewà ti ara rè. Òsèré yí dàbí eni tí inú ...

Read More »

Fayose se ayeye odún ketàdínlógóta (57)ojó ìbí rè pèlú ìsìn ìdúpé ní sóòsì pèlú ìyàwó rè.

   Gómìnà ìpínlè Ekiti Fayose se ìsìn ìdúpé ní gbàgede Lady Jibowu ti ilé ìjoba fún ti ayeye odún ketàdínlógóta ojó ìbí rè. Àwòrán ibi tí ó ti n dì mó ìyàwó rè.

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb