Home / Art / Àṣà Oòduà / Sayewo Omo Ita, Jaguda Ti Buhari Fi Se Oludamora Nipa Oro To N Lo Nile Igbimo Asofin

Sayewo Omo Ita, Jaguda Ti Buhari Fi Se Oludamora Nipa Oro To N Lo Nile Igbimo Asofin


Honorebu Suleiman A. Kawu ni yii, okan ninu awon omo ile igbimo asofin ti n fo iganna nigba rogbodiyan to waye nile igbimo asofin ni akoko ti Goodluck Jonathan wa lori oye gege bi Aare ile Nigeria olominira.

Maanu yii kan naa wa lara awon ti Aare Muhammadu Buhari ti yan bayii gege bi oludamoran nipa awon oro to n lo nile igbimo asoju sofin ile Nigeria.

Pelu bi oko Aisha se n pariwo wi pe awon eniyan gidi, omoluabi oloselu ati olooto ni awon eniyan ti oun fe ninu isejoba oun, nje awa le pe eniyan ti n fo iganna gege bi omoluabi alaponle bi?

 

Orisun

About admin

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“They Changed Her Name, Stole Her Freedom, But Could Never Take Africa From Her: The Unforgettable Story of Àbáké”

“They Changed Her Name, Stole Her Freedom, But Could Never Take Africa From Her: The Unforgettable Story of Àbáké”

Matilda McCrear lived long enough to become a human bridge between Africa, American slavery, and the modern era. Born in West Africa around 1857, she was captured as a toddler and transported across the Atlantic aboard the Clotilda in 1860—the last known ship to bring enslaved Africans illegally into the United States. Her Yoruba name was Àbáké, meaning “born to be loved by all.” The facial scars on her left cheek, preserved in photographs, marked her as Yoruba. The voyage ...