Home / Art / Àṣà Oòduà / Igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi dun bi oyin

Igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi dun bi oyin

Oba_Lamidi_Olayiwola
Laipe yii ni Oba Lamidi Adeyemi, Alaafin Oyo pe eni odun metadinlogorin. E le ka iroyin naa nibi:

Lara awon foto ojo ibi baba mi-in to te wa lowo ni eyi ti baba ya pelu Olori Badirat Adeyemi, olori baba to kere ju lo.

Bi Oosa Oyo tile ti dagbalagba, Olori Badirat, eni to sese wo ile iwe giga Ifafiti lodun yii ko je ki ara baba o darugbo kiakia pelu awon itoju orisiirisii ti n fi n te baba lorun niyewu. Eleyii to si n mu baba dabi omo tuntun jojolo.

Ti won ba ni Oba wo lo jaye ju laye? Walahi, Oba Lamidi ni!

Orisun

About admin

One comment

  1. Aisha M.B.P.

    Oba Lamidi with his very young child bride.Thats okay I guess cos he’s not from the North of Nig.

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...