Home / Art / Àṣà Oòduà / Arákùnrin Oyinbo yí ló fé ìyàwó rè tí ó jé omo Edo, tí won sì se ìgbéyàwó ìbílè Alárédè.

Arákùnrin Oyinbo yí ló fé ìyàwó rè tí ó jé omo Edo, tí won sì se ìgbéyàwó ìbílè Alárédè.

Òyìnbó kò mà le mú ojú kúrò lórò lára àwon omoge orílè èdè Nìjíríà rárá, nítorí won mò wípé arewà ni won, won sì mo ìké oko se, bí kò bá jé béè ogún-l’ógbòn àwon òyìnbó ni ó ti fé omo orílè èdè Nìjíríà yí.
E wo arákùnrin yí níbi ayeye ìgbéyàwó ti ìbílè ti òun àti olorì rè, tí a kò bá rí kò omobìnrin náà rewà ó pò jú, e wo bí ó se dàbí eni wípé won bí Òyìnbó náà mó aso ìbílè náà ni.
Èyí wú ni lórí púpò.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...