Home / Art / Àṣà Oòduà / Àwòrán Ìlú Abeokuta nígbà tí a wò ó láti orí òkè olúmo (olumo rock).

Àwòrán Ìlú Abeokuta nígbà tí a wò ó láti orí òkè olúmo (olumo rock).

Òkè olúmo jé òkè kan gbòógì tí a kò le fi owó ró séyìn nínú àwon òkè tí n be ní orílè èdè Nìjíríà, kìí wá se orílè èdè yí nìkan ni a kò tile fi owó ro séyìn bí kò se wípé káàkiri ilè Adúláwò.
Orí òkè yí ni àwon kan wà tí won sì ti ya àwòrán ilú kan ní ilè Yorùbà, tí ó sì je wípé Yorùbá ni won ñ so níbè àti wípé omo Yorùbá àtàtà ni wón. Orúko ìlú náà a máa jé Abeokuta. Abeokuta ni òkè olúmo wà bóyà torí okè yíì ni won ti so orúko náà, ta ló mò? nítorí àwòrán náà fi hàn wípé abé òkè ímyí ni ìlú náà wà.
Òkè olúmo wà ní ìlú Abeokuta, ogún-l’ógbòn àwon ènìyàn ni won sì ti rin ìrìnàjò lo síbè láti lo wo àwon àrà méèrírí tí ó wà lórí òkè yí.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...