Home / Art / Àṣà Oòduà / Àwòrán omo odún mókàndínlógún (19) tí won mú pèlú orísirísi èyà ara ní Awka.

Àwòrán omo odún mókàndínlógún (19) tí won mú pèlú orísirísi èyà ara ní Awka.


Gégé bí ìròyìn se so, won ti fi ìgò gún omo odún mókàndínlógún (19) yánmayànma látàrí àwon èyà ara tí won bá ní owó rè, won bá omoníka àti ojú ara omo odún mérin okùnrin ní Awka, ìpínlè Anambra.
Afura sí náà, tí a mò sí Ògbéni Sunday Onwebenyi láti Emeziaka Mgbo ní ìjoba ìbíle Ohaukwu ní Ìpínlè Ebonyi, tí ó jéwó wípé òun pa omo náà pèlú àwon afura sí míràn ní ibì kan nàà.
Èyí selè nígbà tí òré bìnrin láti agbègbè kan náà tí n jé, omidan Blessing Eze, ni ó ti so fún kí ó lo sí àdúgbò kan ní ìlú Awka, níbi tí owó ti tè é, èróngbà won ni láti tún rí owó púpò si.
Won ti fáà fún àwon olópàá fún Ìwàdìí tí ó tó.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...