Home / Author Archives: Awoyemi Bamimore (page 25)

Author Archives: Awoyemi Bamimore

Maryam Sanda ti sun ekún àsun-n-dáké nígbà tí won gbe lo sí ilé-ejó látàrí ikú tí ó se pa oko rè Billyaminu Bello.

    Maryam Sanda tí won fi èsùn kàn wípé ó gún oko rè Bilyaminu Bello tí ó jé omo alága egbé PDP télè, Haliru Bello pa ní ilé won ní Abuja ní ojó àìkú (Sunday) tí ó kojá, ni ...

Read More »

Arábìnrin yí se ayeye ojó-ìbí fún omo òdò rè ní àrà òtò.

   Èyin obìnrin n’ílé, èèyàn mélòó ni ó le se eléyìí fún omo òdò rè. Omodé yí àti olówó rè rè é nínú àwòrán yí, àná ni ojó ìbí rè. E jòwó obìnrin mélòó ni ó tún le se èyí ...

Read More »

Àwon òrébìnrin tí ó lóyún ní ìgba kan náà ni won ya àwòrán pèlú oyún won.

Àwon òrébìnrin tí ó lóyún ní ìgba kan náà ni won ya àwòrán pèlú oyún won. Eléyìí ma ti è wuni won sì rewà pèlú oyún won papò. Mo ro wípé oyún kìí mú àwon èlòmíràn rewà ni, bí ti ...

Read More »

Iyabo Ojo dùn nínú aso tí kò bo ìdodo (crop top) tí ó wò.

Ògbó-n-tarìgì òsèré, Iyabo Ojo ti gbe lo sí orí èro ayélujára (Instagram) láti àwòrán ara rè nígbà tí ó ti pé ogójì odún tán , ó sì tún fi hàn wípé dunú. Òsèré Iyabo Ojo, yó se ayeye ogójì (40) ...

Read More »

Gomina Obiano lo kí Ààre Buhari ní Abuja léyìn tí ó gbégbà orókè níbi ètò ìdìbò tí won sèsè dì tán ní Anambra.

Gómìná ti ìpínlè Anambra tuntun, Gómìnà Willie Obiano ní ojó etì (Friday ) ti lo kí Ààre Muhammadu Buhari ní ilé-ìjoba ní ìlú Abuja. Obiano ti dúpé lówó Buhari nítorí kò se àgàbà-n-gebè níbi ètò ìdìbò tí ó kojá ní ...

Read More »

Arábìnrin yí ni ó jí èro ìbánisòrò ogbòn (30) tí ó sì ko pamó sí inú kómú àti pátá rè.

Arábìnrin yí ni ó jí èro ìbánisòrò ogbòn (30) tí ó sì ko pamó sí inú kómú àti pátá rè. Odóbìnrin tí a kò mo eye tí ó su ú, ni ó jí ju èro ìbánisòrò ogbòn lo tí ó ...

Read More »

Nabila Fash kúnlè Oritsefemi oko rè nígbà tí ó fón Dólà si l’ára ní ibi ayeye kí ó tó di ojó ìgbeyàwó won.

Nabila Fash kúnlè Oritsefemi oko rè nígbà tí ó fón Dólà si l’ára ní ibi ayeye kí ó tó di ojó ìgbeyàwó won. Ìyáwó Oritsefemi, Nabila, wà ní orí ìkúnlè níwájú oko rè nígbà tí ó bá Dólà fun níbi ...

Read More »

Àwòrán kí ó tó di ojó ìgbéyàwó tí ológun yí àti òdóbìnrin tí ó pàdé lórí èro ayélujára (Facebook) ya.

   Isé rí èro ayélujára n se kojá òye èdá… Àwon oko pèlú Aya àfésónà yí ti setán láti di tokotayà ní òsè péréte si léyìn tí won làdé lórí èro ayélujára (Facebook). Gégé bí Ijeoma Nwosu se so, ó ...

Read More »

Flavour àti àwon omo rè obìnrin méjì, Sophia àti Gabrielle Okoli ti ya àwòrán tí ó ya ni lénu .

Gbajúgbajà olórin ìgbàlódé èyí tí a mò sí Flavour ti gbe lo sí orí èro ayélujára láti pín àwòrán àwon omo rè tí ó pè ní olorì, nígbà tí ó se ayeye ojó ìbí rè pèlu Sophia àti Gabrielle.

Read More »

Àwòrán Yvonne Nelson àti Jamie Roberts, bàbá omo rè níbi tí won tí n fi ìfé hàn sí ara won.

   E wo àwòrán èyí tí ó fi ìfé hàn láàrin olólùfé méjì, ògbóntàrigì òsèré orílè èdè Ghana Yvonne Nelson pèlú bàbá omo rè tí ó jé ayà àwòrán láti orílé èdè Britain. Jamie Robert wo okò òfuruufú láti lo ...

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb