OPC Founder Frederick Fasehun passes on at 83
He was admitted to the Lagos State University Teaching Hospital, Ikeja, on Tuesday, but passed on in the early hours of Saturday. He was 83 years old at the time of his death. Sun re o !
Read More »BalogunAdesina Comments Off on OPC Founder Frederick Fasehun passes on at 83
He was admitted to the Lagos State University Teaching Hospital, Ikeja, on Tuesday, but passed on in the early hours of Saturday. He was 83 years old at the time of his death. Sun re o !
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àwòrán télè ti Leo Babarinde Dasilva nígbà tí ó wà ní omo àgbákórùn.
Àwòrán télè ti Leo Babarinde Dasilva nígbà tí ó wà ní omo àgbákórùn. Ní àná tí se ojóbò tí àwon eléyìbó n pè ni Thursday, won ni kí àwon wo èyìn wò. Ará ilé BBNaija télè tí a mò sí ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àwon Jagunjagun tí a mò sí Soldier ti pa ìko àwon Boko Haram ní Arege, Borno, tí won sì gbà àwon ohun ìja olóró ní owó won.
Two Ikò Boko Haram ti fi ojú winá ogun won sì ti bá ogún lo, tí ojú won sì rí méwàá ni ojó kejìlélógbòn osù kokànlá odún 2018 nígbà tí won tún fé se bí ìse won ní Arege ní ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Arákùnrin tí ó n se yahoo ni ó ti ya wèrè nígbá tí bàbá eè kú tán ní ìlú Benin.
Kàyéfì nlá ni ó jé nígbà tí Arákùnrin kan ya wèrè ní ìlú Benin ní ìpínlè Edo. Gégé bí ìròyìn se so, òdókùnrin yí ni won fi èsùn kàn wípé isé kí á máa fi èro gbáni ni ó n ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Mr Harri se ìgbéyawó pèlú ohun èlò orin tí a mò sí guitar ní ìpínlè Eko.
Arákùnrin kan ní orílè èdè Nìjíríà ti ya òpò èyan lénu látàrí sése ìgbéyàwó pèlú ohun èlò orin tí a mò sí guitar rè. Tí e bá rò wípé e ti ri tán , eléyìí tún ya ni lénu ò. ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Olùsò àgùntàn tí a mò sí pásítò Adeboye tí ó jé olórí àwon omo léyìn Jésù ti ìjo RCCG fún àwon akékòó ìmò adajó tí ó yege jùlo mérin ní Fìlà orí ri awon adájó àti aso won.
Olórí àwon olùfokànsìn àti omo léyì jésù ti Ìjo àwon RCCG, gbogbo àgbáyé, Pásítò E.A Adeboye fún àwon akékòó tí won sèsè gboyè gégé bíi adájó mérin nínú ìjo rè ní àgbàlá HALL OF MERCY, Bwari ní ìpínlè Abuja, ní ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àwon àwòrán tí ó rewà tí Lota Chukwu fi se ayeye ojó ìbí rè nígbá tí ó pé omo odún mókàndínlógbòn (29).
Àwon àwòrán tí ó rewà tí Lota Chukwu fi se ayeye ojó ìbí rè nígbá tí ó pé omo odún mókàndínlógbòn (29). Gbajúgbajà arewà òsèré orílè èdè Nìjíríà tí ó n jé Lota Chukwu se ayeye odún mókàndínlógbon ojó ìbí ...
Read More »BalogunAdesina Comments Off on Syrian War Report – Nov. 29, 2018: US Is Establishing ‘Observation Posts’ On Syrian-Turkish Border
On November 28, Russian air-defense forces deployed intercepted and destroyed an unmanned aerial vehicle (UAV) near the Russian Hmeimim airbase in the province of Lattakia, according to local sources. The intercepted UAV was probably an armed UAV launched by militants ...
Read More »BalogunAdesina Comments Off on Updated: Syrian Air Defense Forces Shoot Down “enemy Objects” Over Damascus
UPDATE: the Israeli military said on Twitter: During a Syrian surface-to-air missile launching, one launch was identified towards an open area in the Golan Heights. At this point, it remains unclear if the launch indeed landed in Israeli territory. IDF troops ...
Read More »BalogunAdesina Comments Off on Argentina and France – Opponents of IMF versus Yellow Vests – Where is the Correlation?
by Peter Koenig What do Argentinian protesters have in common with French protesters? – They both strongly dislike their governments, and their leaders (sic). The protests in Argentina against the upcoming G20 meeting and around the IMF are just a ...
Read More »
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more