Home / Art (page 78)

Art

Arákùnrin tí ó jé omo Ebonyi, ìpínlè kan ní orílè èdè Nìjíríà yí ti kú sí ilè Italy pélù àwon mókànlá míràn.

Èyí bani ní inú jé púpò, arákùnrin tí ó jé omo orílè èdè Nìjíríà yí ti kú pèlú àwon mókànlà míràn ní inú ìjàmbá okò tí ó selè ní Foggia ní ilè Italy. Gégé bí ìròyìn se so, olóògbé yí, ...

Read More »

Omobìnrin kékeré yí ni won dáné sun nígbà tí won fi èsùn kàn án wípé àjé ni, ní ìpínlè Akwa Ibom.

Àwòrán tí ó wà ní ìsàlé yí ni àwòrán omobìnrin kan tí orúko rè a máa jé Queen, won dáné sun omo yí látàrí èsún tí won fi kàn án wípé Àjé ni. Anja Louvre tí ó jé panépané ní ...

Read More »

Àràbà Aworeni Adisa Makoranwale sun re.

òní tí ó jé ojó kokànlá osù kejo odún 2018 (11/8/2018) ni ètò ìgbé òkú baba wa tí ó sísè ní ojo ìségun tí ó jé ojó kokànlél’ógbòn osú keje odún tí a wà (31/7/2018) sí isà . Ìjo International ...

Read More »

Timi Dakolo pín àwòrán ti ó rewà ti ìyàwó rè pèlú omo méta ní London.

Gbajúgbajà olórin ti orílè èdè Nìjíríà, Timi Dakolo ti pín àwòrán ìyàwó rè àti àwon omo rè méta ní ìlú London, ó ko síbè wípé “wón tun ti dé baba wón tún ti dé”. Timi Dakolo ti ó jé omo ...

Read More »

Olorì Badirat Olaitan, ìyàwó Aláàfin Òyó kéreké parí ilé-èkó gíga ifáfatì ti ìlú ìbàdàn (university of Ibadan).

Olorì Badirat Olaitan, ìyàwó Aláàfin Òyó, Oba Lamidi Adeyemi kékeré, ti parí ifáfitì ní ilé-èkó gíga ifáfitì ti ìlú Ibadan tí a mò sí University of Ibadan. Bí omo bá dára ká so, ó ye kí á yé olorì sí ...

Read More »

Ilé Ẹjọ́ Gíga Orílẹ̀-Èdè Braṣil: Ẹ Dáàbò bo Ẹ̀sìn Ìbílẹ̀ Aláwọ̀ Dúdú (Yoruba version by Akin Ogundiran)

Ilé Ẹjọ́ Gíga Orílẹ̀-Èdè Braṣil: Ẹ Dáàbò bo Ẹ̀sìn Ìbílẹ̀ Aláwọ̀ Dúdú (Yoruba version by Akin Ogundiran) Àbádòfin kan ti kalẹ̀ ní ìlú Rio Grande do Sul ní ilẹ̀ Braṣil tí yô ká àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ aláwọ̀dúdú lọ́wọ́kò láti máa ...

Read More »
Labalaba

Labalaba

  Ope, Awo Labalaba Adifa fun Labalaba Eyi tii se Ojise Olódùmarè Ope ni won ni ki o maa se A ni t’inu t’eyin mi re o, Olódùmarè Labalaba kii sede A ni t’inu t’eyin mi re o, Olódùmarè Gratitude, ...

Read More »
esu

ÈSÙ (Olá ìlú, Bàkeré, Oláàróyè)

  Keesu gbà, kebo óda félébo Adia’fun òyìnbó olomo atùkólókò Olomo agberebete lori irebete Njé ìgbà Òrúnmìlà fòrúlá jekà Kéésù gbà, kebo oda felebó Praise~ Olórógun òde Láaróyè agòngò lagò Alamulamu bata Ofebata kojo lamulamu, seketepere Onile ojude,okunrin firifiri japi ...

Read More »

Yoruba heart and mind in a Frenchman’s body!

Remembering Pa Pierre Fátúmbí Verger, the polymath… Pa Pierre Fátúmbí Verger was born French into a noble lineage and this great man devoted more than half of his 93-year life to the study, promotion, development and practice of Yoruba culture. ...

Read More »
araba adisa

Photo: Araba Adisa Mokorowale with Prof. Moyo Okediji July 26, 2017.

Adieu He was never stingy with his knowledge without asking for a penny. He was patient, kind and nurturing. He taught me more than I could handle and gave me unfettered access to his entire resources. Ó di gbéré Ó ...

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb