Olùkó̩ni Arteta ti rí ìwòsàn Lati owo Akinwale Taophic Olukoni fun egbe agbaboolu Arsenal ni orileede England, eni ti okiki kan kaakiri ni bi ose meji seyin wi pe o ti ni aisan Coronavirus, Mikel Arteta, ni o ti je ...
Read More »Manchester United Ti Se Tán Láti Ra Odion Ighalo Pátápátá
Manchester united ti se tán láti ra Odion Ighalo pátápátá Lati owo Akinwale Taophic Se won ni ti egungun eni ba jo re, ori a ma ya atokun re. Ati wi pe, Ku ise ni n mu ori eni ya! ...
Read More »Ronaldinho Ń Kó̩ Is̩é̩ Gbé̩nàgbe̩nà Nínú È̩wò̩n Ní Orílèèdè Paraguay
Ogbontarigi ninu boolu alafesegba to je omo bibi orileede Brazil ti o si ti fi igbakan ri je eni akoko ninu boolu alafesegba kaakiri agbaye, Ronaldinho,
Read More »A Rising Tide: In Defense of Socialist Billionaires
In order to understand why the phrase “socialist billionaire” is not an oxymoron, it is important to clarify the difference between the two economic systems.
Read More »Nigerian Capitalist Billionaires Busy Counting Losses As 6.6 Million Face Masks, Kits Donated By A ‘Socialist Billionaire’ Jack Ma Arrive Lagos!
The donation to African countries by Jack Ma, founder of Alibaba Group, has arrived Lagos amid the coronavirus outbreak. This came as Nigerian billionaires including clerics, politicians and businessmen, were yet to individually or collectively announce plan to assist Nigerians. The ...
Read More »Nigeria Coronavirus Cases Rise To 44
The Nigeria Centre for Disease Control has announced two new cases of coronavirus, bringing the total number of persons infected in the country to 44. The NCDC made this known via its Twitter handle on Tuesday. NCDC tweeted, “Two new ...
Read More »Àfàìmọ̀ Kí Coronavirus Má Dà Bí I Ti China Tabi Italy- Mínísítà Kìlọ̀
Ẹni mẹ́rin mì ìn kó àrùn apinni ní mímí èèmii coronavirus ní Nàìjíríà,àfàmọ̀ kò mọ́ dà bí i ti China,l Italy— Mínísítà kìlọ̀ Fẹ́mi Akínṣọlá Ìgbọrọ̀ sàn ju ẹbọ rúrú fún ẹni tó bá fẹ́ gbọ́ ni o.Ó ti di ...
Read More »E̩ Fi Àdúrà Rànmí Lọ́wọ́, Nítorí Ọmọkùnrin Mi Ti Lùgbàdi Àrùn Coronavirus … Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀ Yìí Nígbà Kan
Ẹ fi àdúrà rànmí lọ́wọ́, nítorí ọmọkùnrin mi ti lùgbàdi àrùn coronavirus … igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀ yìí nígbà kan
Read More »Àwọn Fíìmù Òde Òní Ń Kọ́mọ Lólè Àti Ọ̀pọ̀ Ìwà Burúkú – Iyabo Ogunsola
Àwọn fíìmù òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú Fẹ́mi AkínṣọláṢé àwọn àgbà bọ̀ wọ́n ní ẹgbẹ́ burúkú ba ìwà rere jẹ́. Ajíyìnrere Felicia Iyabode Ogunsola tí gbogbo èèyàn mọ̀ sí Efúnsetán Aníwúrà, Ìyálọ́de ìlú Ìbàdàn nínú eré, ...
Read More »Ènìyàn O̩gbò̩n Ti Lùgbàdì Coronavirus Ni Naijiria
Ènìyàn o̩gbò̩n ti lùgbàdì coronavirus ni NaijiriaÌròyìn láti o̩wo̩ Yínká Àlàbí Afi ki Eledua maa ko wa yo ni orileede yii. Bi ere bi awada, ajakale arun kogboogun (covid-19) ti mu eniyan ogbon di asiko ti a n ko iroyin ...
Read More »