Home / Art / Àṣà Oòduà / Àwon Jagunjagun tí a mò sí Soldier ti pa ìko àwon Boko Haram ní Arege, Borno, tí won sì gbà àwon ohun ìja olóró ní owó won.

Àwon Jagunjagun tí a mò sí Soldier ti pa ìko àwon Boko Haram ní Arege, Borno, tí won sì gbà àwon ohun ìja olóró ní owó won.

Two Ikò Boko Haram ti fi ojú winá ogun won sì ti bá ogún lo, tí ojú won sì rí méwàá ni ojó kejìlélógbòn osù kokànlá odún 2018 nígbà tí won tún fé se bí ìse won ní Arege ní ìjoba ìbílè Mobbar ní ìpínlè Borno.
Àwon akoni wa ti kojú ogún dàwón won sì ti jéyán won nísu.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

yemoja 2026

Yoruba Yemoja float with 10,000 Litres of water by Mocidade Alegre Won the São Paulo Carnival 2026 in Brazil!

This majestic allegorical float, a viral sensation during the parade, featured Yemoja (Iemanjá) Yemoja was powerfully incorporated because the enredo “Malunga Léa – Rapsódia de uma Deusa Negra” was a heartfelt tribute to the late legendary Brazilian actress Léa Garcia (1930–2023). A pioneering African icon in theater, film, and TV (famous for roles like in Escrava Isaura and her work with Teatro Experimental do Negro). The theme celebrated her as a “deusa negra” (“Black” Goddess): her resilience, ancestral strength, female ...