Home / News From Nigeria / Breaking News / Àwòrán tuntun tokotayà tí won sèsè fé ara won léyìn tí won ti wà gégé bí Òré tímótímó.

Àwòrán tuntun tokotayà tí won sèsè fé ara won léyìn tí won ti wà gégé bí Òré tímótímó.

Àwòrán kí ó tó di ojó ìgbeyàwó olùgbá bóòlù aláwòn ní Brooklyn, Quincy Acy àti àfésónà rè, Jessica Fuenten tí ó sèsè gbòde kan léyìn ìgbà tí inú arewà ìyàwó àfésónà sì ń dùn, so wípé àwon bèrè gégé bíi Òré tímótímó. Àtìgbà tí àwon ti fé ara àwon, àwon ń gbé pèlú ìdùnú gégé bí a ti ri nínú àwòrán ìsàlè yìí. E wo irú ìdùnú tí omobìnrin yí kò bá pàdánù tí kò bá gbà kí won fé ara won sùgbón tí won jo jé Òré Lásán …

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...