Home / Art / Àṣà Oòduà / Fatai Owoseni sàkóso lílo bíbò ní Ikorodu láti owó omo oòduà rere !
Fatai Owoseni

Fatai Owoseni sàkóso lílo bíbò ní Ikorodu láti owó omo oòduà rere !

Kàyééfi ńlá gbáà ni súnkere fàkere okò tí ó selè ní ìròlé àná ní bóòsì dúró Agric (Agric bus stop), Ikorodu ní ìlú Èkó. Tí ó kan ògá pátápátá ilé-isé olóòpá (commissioner of police) Ògbéni Fatai Owoseni láti yo òpòlopò ènìyàn nínú súnkere fàkere tí ó selè ní bóòsì dúró Agric.
 
Gégé bí ìròyìn se so àwon ò n tajá àti ò n rajà ti férè gba ìlàjì ojú ònà tán, tí won sì fi ònà díè sílè fún àwon tí ó ni ònà, èyí fa ìdádúró púpò fún òpòlopò ènìyàn tí àwon míràn sì dúró sinsin.
 
Nígbà tí Ògá olóòpá (CP) ń bò láti Ikorodu ó sò kalè láti rìn lo sí bóòsì dúró (bus stop) láti mo ohun tí ó fà á.
 
Nígbà tí LASTMA tí kò leè gba ara rè sílè, àti àwon tí ó ń darí maalo maabò àti ìgbìmò egbé awakò (NURTW) dúró láìrí nkankan se, ògá olóòpá àti àwon emèwà rè lé àwon tí ó ń tajà ní ojú ònà yí kúrò tí gbogbo rè sì lo sí rowó rosè kí ó tó kúrò lo sí Ikeja.
Kò saláì fi ìkìlò sílè kí ó tó lo wípé ohun kò fé rí àwon olójà kankan ní ojú ònà mó láéláé…..

English Version
Contnue after the page break

About ayangalu

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...