Home / Art / Àṣà Oòduà / Kí ni ojú ò rírí, kárí ká f’ojú fò lópò. Njé Eléhà ninèyí tàbí Egúngún?.

Kí ni ojú ò rírí, kárí ká f’ojú fò lópò. Njé Eléhà ninèyí tàbí Egúngún?.

Òrò náà só síni lénu ó tún buyò si, àbí bí èèyàn yóò bá jé òsákálá kí ó jé Òsákálá bí yóò sì jé Òsokolo kí ó ké Òsokolo, èwo ni òsákálásokolo. Èyí èèyàn sé Eléhà ni a ó pe eléyìí ni àbí Egúngún?. Eléyìí kojá òyé ti èmi.
Kí á ti è má fa òrò gún kò kúkú sí ìyàtò láàrin àwon méjèjì, èkú oko ni ìyàwó rè n wò kiri.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Lati Ọwọ Aworosaṣa Moyọ Okediji

Cultural War Rages on: Africa’s Civilizations Are Being Erased—who Will Teach African Artists?

AFRICAN AESTHETICS Many universities in the West are developing core curriculum programs focused on “Western Civilization,” while increasingly purging African, African Diaspora, Asian, and other civilizations from their programs. The West focusing on Western Civilization is appropriate. The days of African and African Diaspora Studies seem numbered. At the same time, Africana artists are producing contemporary works like never before. What are these Africana artists going to read? Are they going to study Western Civilization only, without any understanding of ...