Home / News From Nigeria / Breaking News / Odómokùnrin ilé-èkó girama ya Òrébìnrin rè lénu nípa èbùn ojó-ìbí tí ó fun tí ó sì fi gba ìfenukonu.

Odómokùnrin ilé-èkó girama ya Òrébìnrin rè lénu nípa èbùn ojó-ìbí tí ó fun tí ó sì fi gba ìfenukonu.

Àwòrán yí tí Òrékùnrin àti Òrébìnrin ilé-èkó girama ní bi tí won ti ń fi enu ko ara won lénu kárakára tí ó sì ti gbòde kan. Níbi àwòrán yìí arí àwon akékòó nísìírí sí omokùnrin náà bí ó se gbé èbùn ojó-ìbí náà fún olólùfé rè. Níbèrè Pèpè, ojú kókó ń ti omobìnrin náà sùgbón léyìn ìsírí tí àwon Òré rè fun, ó fa okùnrin náà móra ósì fi enu kò ó lénu.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...