Home / Art / Àṣà Oòduà / Odún pé, odún jo, àmòdún wa èsín pé.

Odún pé, odún jo, àmòdún wa èsín pé.


Ikú bàbá yèyé, Aláse èkejì Òrìsà, baba wa Aláàfin ti ilè Òyò, Oba Lamidi Adeyemi 111 se ayeye ojó ìbí rè ní òní tí won pé ogórin odún (80).
Àrà méèrírí ni kábíèsí, Ikú bàbá yèyé nítorí baba ni wón lójó gbogbo. Won kò sí jé kí Àsà Yorùbá parun rárá, won n gbé Àsà láruge nígba gbogbo.
Òmo oòdua kí Aláàfin kú àjòdún ojó ìbí won, baba kí e pé ooo.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Happy New Calendar Year!!! It is 10068 of the Oodua Yoruba Calendar-–-KỌ́JỌ́DÁ

The Yoruba traditional calendar, called Kọ́jọ́dá, starts the new year on June 3rd and ends on June 2nd the following year. It’s a lunar calendar with a 4-day week (each day honoring different Orisa), 7 weeks in a month, and 13 months in a year—so their year is 364 days long. The months and weeks are deeply tied to farming cycles, moon phases, and religious rituals.The traditional Yoruba week has four days. The four days that are dedicated to the ...