Home / Art / Àṣà Oòduà / Odún pé, odún jo, àmòdún wa èsín pé.

Odún pé, odún jo, àmòdún wa èsín pé.


Ikú bàbá yèyé, Aláse èkejì Òrìsà, baba wa Aláàfin ti ilè Òyò, Oba Lamidi Adeyemi 111 se ayeye ojó ìbí rè ní òní tí won pé ogórin odún (80).
Àrà méèrírí ni kábíèsí, Ikú bàbá yèyé nítorí baba ni wón lójó gbogbo. Won kò sí jé kí Àsà Yorùbá parun rárá, won n gbé Àsà láruge nígba gbogbo.
Òmo oòdua kí Aláàfin kú àjòdún ojó ìbí won, baba kí e pé ooo.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

What is Àdìmù?

A few of my friends and students in the diaspora had asked me this question countless times, and I think it’s high time we discussed it.Please note that this is not an attempt to discredit or invalidate any practice or belief; this piece is just for us to educate one another.Now, in the Yoruba language, what does Adimu mean, or where does it originate from?Àdimu means “To hold.”The full word is Adimula, which means “to hold and prosper.”So, where does ...