Home / Art / Àṣà Oòduà / Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ìsèlè burúkú gbáà ní Óní selè ní ojó kewàá osù keje odún 1999 ní ilé-èkó gíga ifáfitì Obafemi Awolowo university nígbà tí èmi oní inú ire sì gba ibè lo.

Afrika se béè Ó ta èjè rè sílè fún àwon akékòó ilé-èkó yí láti dènà egbé òkùnkùn láti ìgbà náà ni àláfíà, ìfòkànbalè ti wà nínú ogbà yí. Njé ó wá ye kí á gbàgbé ojó yí bí?

Èní lópé odún mókàndínlógún tí Afrika kú fún wa, kí ló wá dé tí a kò le polongo “kí egbé òkùnkùn wá sí òpin ” kí lódé tí a kò le rántí èjè tí Óní kú fún akékòó?

Akoni ni Afrika ejé kí á se ayeye ìrántí fun, kí á kí àwon ebí rè wípé wón kú afárárekù eni rere..

Njé Ìwo tí setán láti gbógun ti egbé òkùnkùn bí?.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...