Home / Art / Àṣà Oòduà / Omobìnrin kékeré yí ni won dáné sun nígbà tí won fi èsùn kàn án wípé àjé ni, ní ìpínlè Akwa Ibom.

Omobìnrin kékeré yí ni won dáné sun nígbà tí won fi èsùn kàn án wípé àjé ni, ní ìpínlè Akwa Ibom.

Àwòrán tí ó wà ní ìsàlé yí ni àwòrán omobìnrin kan tí orúko rè a máa jé Queen, won dáné sun omo yí látàrí èsún tí won fi kàn án wípé Àjé ni.

Anja Louvre tí ó jé panépané ní ìpínlè Akwa Ibom ní ó gba omobìnrin yí kalè, tí kò sì jé kí ó kú ikú òjijì.

Ó gba omobìnrin yí kalé kí ó tó di wípé ó gbé èmí mì nígbà tí àwon èèyàn rè dáné sún ún ní ó kojá odún kan séyín.

Arábìnrin òsìsé Danish yí ni ó pín àwòrán yí sí orí èro ayélujára rè, tí ó sì ko isé tí ìgbìmò won n se síbè, nígbá rí ó jé wípé ètó won ni láti ran àwon lówó bí ti Queen.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...