Home / Art / Àṣà Oòduà / Owó te olùsó àgùntàn(pastor) èké kan nígbà tí ó ń gbìyànjú láti ri ohun tí a kò mò sí ilé onílé. 
pasito

Owó te olùsó àgùntàn(pastor) èké kan nígbà tí ó ń gbìyànjú láti ri ohun tí a kò mò sí ilé onílé. 

Olùsó àgùntàn èké kan tí a mò sí Osinachi Christopher láti ìpínlè Abia ni won fi s’èsín léyìn ìgbà tí owó ti tèé nígbà tí ó ń gbìyànjú à ti ri ohun tí a kò mò sí ilé onílé ní agbègbè Nnobi ní ìpínlè Anambra . Gégé bí eni tí ó pin se so èyí kó ni àkókó tí Olùsó àgùntàn náà ma se èyí.

Ka ohun tí Uzochukwu Onuabuchi so ní ojó etì tí ó kojá, ojó ketàlélógún osù kefà (Friday, June 23rd)

Ojú kò kú ní yé rí, ìyanu kò sì le dópin .Olùsó àgùntàn Osinachi Christopher rè é láti Isuochi ní ìpínlè Anambra,  owó tè é nígbà tí ó fé ri ohun tí a kò mò sí ilé onílé, tí won ma padà gbé jáde l’órúko ìdílé náà, ó tún jéwó wípé sisé pèlú Olùsó àgùntàn kan tí orúko rè ńjé Miracle Ihuoma.

Ó tún jéwó wípé. Olùsó àgùntàn èké Miracle ri ohun tí a kò mò sí iwájú ìsò Alabi kan tí ó jé ìyàwó Makosa. Olùsó àgùntàn yí tún wá so fún arabìnrin yí wípé Olùsó àgùntàn ti télè Ebubedike ni ó ri ohun náà síbè. Ònà èké yí ni ó gbà láti lé Ebubedike lo. Ebubedike tí olórun ti ń lò fún isé ìyanu ní Nnobi.

Ohun kan tí èmi mò láyé ni pé kò sí ohun tí ó pamó lábé òrun. Olórun ti fi Olùsó àgùntàn èké Miracle Ihuoma hàn , tí ó ní Ìjo ní Makosa ní Ifite Nnobi ní ìpínlè Anambra.

Gégé bí Olùsó àgùntàn èké Osinachi nínú àwòrán àti Miracle Ihuoma. Ó seoooooo ……

Continue after the page break for English version

About ayangalu

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...