Kí á dijú ká se bí eni tí ó kú kí á wo eni tí yó se ìdárò eni Ká fi esè ko gbàù kí á wo eni tí yó seni pèlé Ayé laó ti mo eni tí ó ń ...
Read More »
Awoyemi Bamimore Comments Off on Alágemo tó se jéjé ikú pa á.
Kí á dijú ká se bí eni tí ó kú kí á wo eni tí yó se ìdárò eni Ká fi esè ko gbàù kí á wo eni tí yó seni pèlé Ayé laó ti mo eni tí ó ń ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Grace Oyelude, obìnrin àkókó tí Ó kókó gba àmì èye omidan arewà ní orílè èdè Nìjíríà.
Grace Oyelude, obìnrin àkókó tí Ó kókó gba àmì èye omidan arewà ní orílè èdè Nìjíríà. Ìyáawa Grace Atinuke, tí won bí ní ojó kerìndínlógún osù beelu ní odún 1931, tí a mò sí eni tí ó kókó gba àmì ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Irú kí ni eléyìí báyìí, àfi kí olúwa olódùmarè .
Nìjíríà àfi kí olórun gbà wá lówó gbogbo hílàhílo tí ó ń selè yí, irú kí leléyìí báyìí . Eléyìí ló selè ní Oghara. arábìnrin kan ni ó ún gun òkadà lo tí ó sì gbé epo beetíròlù séyìn nígbà ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).
Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU). Ìsèlè burúkú gbáà ní Óní selè ní ojó kewàá osù keje odún 1999 ní ilé-èkó gíga ifáfitì Obafemi Awolowo university nígbà tí èmi oní inú ire sì gba ibè lo. Afrika ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on AJE NIMO FẸẸ!
. AJE NIMO FẸẸ! Ohun aje f’oju miri ẹnu o le sọ; Oju miri to lori ọrọ aje; Owo(business) f’ẹgbin rẹmi lara; Ninu ẹgbin lọla fiṣe ile; Ọrọ kobakungbe inu iṣẹ-aje ni ngbe. Aje ogugu ni sọ; Onisọ iboji o; ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Ogbón kò kúkú ní tán n’ílé ayé kí á wa lo sí òde òrun.
Ogbón kò kúkú ní tán n’ílé ayé kí á wa lo sí òde òrun. Arákùnrin kan ni ó so àwon táyà okò tí ó ti bàjé yí di tábìlì aláfé, okùnrin yí tí ó jé omo orílè èdè Nìjíríà. Kí ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àwon ìbeta tí ó rewà yí tí ewà won sì wuni yí se ayeye ojó ìbí won pèlú àwòrán tó yááyì.
John, Peter àti Jamie Obidiegwu, ìbeta se ayeye ojó ìbí won ní àrà òtò. Ayeye ojó ìbí míràn ni ó jé fún àwon ìbeta tí ó jé okùnrin yí, ohun ayò ni ayeye yí sì jé fún won tí won ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Ìgbeyàwó alárédè ti DJ consequences àti Olayemisi Williams.
Arákùnrin tí ó ń se isé DJ tí a mò sí DJ consequences àti aya rè Olayemisi Williams ti se ayeye ìgbeyàwó won. A kí tokotayà kú oríre .
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Tboss se ayeye ojó ìbí fún ìyá rè àgbà ti ilè Roman
Tboss se ayeye ojó ìbí fún ìyá rè àgbà ti ilè Roman. Ará ilé télè ti BBnaija tí a mò sí Tokunbo Idowu tí ìnagije rè ń jé Tboss, ti se ayeye ojó ìbí fún ìyá rè àgbà ti ilè ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àgbàrá òjò gbé èèyàn méjì lo ní UNN, Nsukka, tí ó sì pa wón.
Èèyàn méjì òtòtò ni ó di olóògbé látàrí àgbàrá òjò tí Ó gbé won lo, tí Óní sì pa wón sí gbàgede enu àbáwolé ilé-èkó gíga ifáfitì ti orílè èdè Nìjíríà, Nsukka (UNN). Gégé bí ìròyìn se so àwon olóògbé ...
Read More »
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more