Home / Art / Àṣà Oòduà / Gáàsì bú gbàmù ní Cross river tí ó sì pa èèyàn méji, tí ó fa ìpalára fún àwon mérin nínú ebí.
gassi

Gáàsì bú gbàmù ní Cross river tí ó sì pa èèyàn méji, tí ó fa ìpalára fún àwon mérin nínú ebí.

Àwon omo ebí mérin ti igbákejì adarí kíko eré ìdárayá ní orílè èdè Nàìjíríà ” Vice President of Sport Association (SWAN), Eddie Bekom tí a gbà sí ilé-ìwòsàn léyìn ìgbà tí gáàsì tí wón fi ń dáná bú gbàmù láti òdò alámúlé gbè won ní Ikom, Ní ìpínlè Cross river.
Bekom, ìyàwó rè àti àwon omo mérin won nígbà tí Ìsèlè náà selè. Won kókó ń tójú won ní ilé-ìwòsàn ní Ikom télè kí ó tó di wípé won gbe lo sí ilé-ìwòsàn ńlá ní Abakaliki fún ìtójú elékèejì.

Ó se ni láànú, ìyàwó Bekom àti ìkan nínú àwon omo rè ti kú látàrí Ìsèlè yí. Ìròyìn so wípé owó tí ó tó mílíònù méwàá (#10 million) ni wón nílò fún ìtójú won. .

Continue bellow for the English translation

About ayangalu

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...