Home / Art / Àṣà Oòduà / Odún dé, ore yèyé òsun.

Odún dé, ore yèyé òsun.

Òsun Osogbo tún ti dé lónìí tí se ojó ketaàdínlógún osù kejo odún, 2018, tí gbogbo àgbàyé fi n se odún fún Òsun éléyinjú àánú, igbómolè obìnrin

Òsàyòmolè
Nílé ìyà olúgbón won kò gbodò mawo
Ìran arèsè kò gbodò morò
Olúwa mi ló morò lósì mopa
Òsun lo mopa tééré tí í pa won jé…

Ore yèyé òsun oooo
A kí yín kú odún lénìí, àsèyí se àmódún àse àmódún se èmíì.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...