Home / Art / Àṣà Oòduà / Maryam Sanda ṣì wà lẹ́wọ̀n, Buhari kò dáa sílẹ̀.
Maryam Sanda

Maryam Sanda ṣì wà lẹ́wọ̀n, Buhari kò dáa sílẹ̀.

Iléeṣẹ́ Ààrẹ ló sọ pé Ìròyìn tó ń jà rànyìnrànyìn kiri pé Ààrẹ Muhammadu Buhari tí darí jin arábìnrin náà kìí ṣe òtítọ́ rárá.Ki àwọn èèyàn kọtí ọ̀gbọin sí i.
Ní oṣù kínní ọdún yìí ni ilé ẹjọ́ dá arábìnrin Maryam Sanda lẹ́bi ikú pé ó jẹ̀bi ẹ̀sùn gígún ọkọ rẹ̀ pa tí wọ́n fi kàn án.

Amúgbálẹ́ẹ̀gbẹ́ fún Ààrẹ Buhari lórí ọ̀rọ̀ Ìròyìn ayélujára, Bashir Ahmad ló fi síta lójú òpó twitter rẹ̀ pé, ara ọ̀nà láti ba orúkọ rere tí Ààrẹ ti ní lórí ètò ìdáríjì fáwọn ẹlẹ́wọ́n tó wáyé láìpẹ́ yìí lọ́nà àti mú àdínkù bá àwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n tó kún fọ́fọ́ lórílẹ̀-èdè yìí.

Fẹ́mi Akínṣọlá

About ayangalu

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...