Home / News From Nigeria / Breaking News (page 140)

Breaking News

Won ti ojà ní Abeokuta láti fi se àpónlé fún Oba won tí ó di olóògbé.

Ojà tí ó wà ní ìlú Abeokuta ní won tì pa pátápátá ní àná, won se èyí láti fi se àpónlé Oba won tí ó wàjà eni tí a mò sí Oba Halidu Laloko (MFR) tí ó jé Agura ti ...

Read More »

Tuface àti àwon omo rè okùnrin méjì Nino àti Ziona Idibia ní New York.

Tuface àti àwon omo rè okùnrin méjì Nino àti Ziona Idibia ní New York. Gbajúgbajà tí ó tún jé ògbóntarìgì olórin ìgbàlódé ti a mò sí Tuface Idibia tí ó wà ní orílè èdè United State báyìí fún ìrìn àjò ...

Read More »

Àwon ajínigbé àti omo egbé òkùnkùn mérin ní ìpínlè River

Àwon ajínigbé mérin tí won tún jé omo egbé òkùnkùn tí ńkó da ìjoba ìbílè Eleme àti agbègbè rè láàmú ni àwon olùbódàbòbò pa . Orúko àwon tí won pa a máa jé Joe Mba tí ìnagije rè ńjé Sk ...

Read More »

Alibaba tako Anthony Joshua nígbà tí ó ya àwòrán Láì wo aso tí àwon èyà ara rè sì hàn.

Anthony Joshua ní láti gbáradì fún ogun míràn báyìí ni Alibaba tí Ó jé apanilérìn-ín àti adérìn-ín pa òsónú se so nígbà tí Anthony fi aya rè hàn tí èyí sì fi hàn wípé okùnrin mésàn-án ni, òun náà sì ...

Read More »

Falz – Child Of The World

‘Child Of The World’ is taken from the 3rd Solo Studio album by FalzTheBahdGuy Boogie: https://youtu.be/8LR7KaP1mZs Next: https://youtu.be/ErqS752vQ_k This Is Nigeria: https://youtu.be/UW_xEqCWrm0 Foreign: https://youtu.be/di8TMOVmQro Way: https://youtu.be/d9mQJS44H-s La Fête: https://youtu.be/4k3XE9uzMVc Something Light: https://youtu.be/Ed6hQrmL_2s Jeje: https://youtu.be/Y4miw7yN5bY Baby Boy: https://youtu.be/ItwCPZ_5OgI Wehdone Sir: https://youtu.be/oBJXKyXhaVw FOLLOW ...

Read More »

Ògún lákáayé .

Ọ̀wọ́nyán rosùn porogodo lóso, Agogo ńlá ni wọ́n fi ń fọ́ri fálágbára mu, Àtàtà ńlá ni wọ́n fi ń fọ yíìrí mọrọ̀, Adífáfún Ògún tíń gbógun lọ sí Ìgbòmẹkùn-eséji, ẹbọ lawo níkóse, Ògún ló sẹbọ sètùtù lówá kóre dé ìtùtúrú ...

Read More »

Àwòrán Saraki nígbà tí won se ìpàdé pèlú Woke, Ortom àti àwon míràn ni ìpínlè Kwara.

Àwon ìgbìmò tuntun rè é, Gómìnà ìpínlè River, Nyesom Ezenwo Wike tètè dé sí Ilorin ní ìpínlè Kwara fún ìpàdé pàtàkí náà pèlú àwon ti Benue náà, Gómìnà Samuel Ortom tí ó sèsè ko ìwé láti fi egbé APC sílè ...

Read More »

Alágemo tó se jéjé ikú pa á.

Kí á dijú ká se bí eni tí ó kú kí á wo eni tí yó se ìdárò eni Ká fi esè ko gbàù kí á wo eni tí yó seni pèlé Ayé laó ti mo eni tí ó ń ...

Read More »

Grace Oyelude, obìnrin àkókó tí Ó kókó gba àmì èye omidan arewà ní orílè èdè Nìjíríà.

Grace Oyelude, obìnrin àkókó tí Ó kókó gba àmì èye omidan arewà ní orílè èdè Nìjíríà. Ìyáawa Grace Atinuke, tí won bí ní ojó kerìndínlógún osù beelu ní odún 1931, tí a mò sí eni tí ó kókó gba àmì ...

Read More »

Awada Toni: Omo Ibadan

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb