Home / News From Nigeria (page 366)

News From Nigeria

Nínú agbami ifè ni won wà, gbajúmò òsèré Mode Funmi Martins àti oko rè Afeez Owo fi ìfé won hàn.

À béè rí nkan, e ri bí won se se jómúrégí papò! Won bá ara won mu gan ni…

Read More »

Àwòrán tí ó ti pé ti gbajúgbajà òsèré Odunlade Adekola.

     Àwòrán ìgbà èwe ni ní tòótó fún gbajúgbajà òsèré Odunlade Adekola. Táà bá ní pa iró owó dáa l’ára…

Read More »

Òdóbìnrin orílè-èdè Nàíjíríà kan se ayeye ojó ìbí rè tí ó sì há oúnje fún àwon aláìní.

    Òdómobìnrin orílè-èdè Nàíjíríà ni ó pinnu láti se ayeye ojó ìbí ní àrà òtò, nígbà tí a ri tí ó n pín oúnje àti àwon nkan míràn fún àwon aláìní, omodé àti àwon èèyàn míràn . ònà ni ...

Read More »

Oba Orin Sunny Ade àti Flavour Jo hàn ní orí ìtàgé.

     Oba orin Sunny Ade àti Flavour dìjo dá àwon ènìyàn l’ára yá lórí ìtàgé. Pèlú èrín ojú Flavour n se ni ó dà bí eni wípé inú rè dùn láti pàdé oba orin…

Read More »

Olùsó àgùntàn David Ibiyeomie gba okò bògìnì fún èbùn ojó ìbí rè nígbà tí ó pé odún márùnléláàdóta .

     Gégé bí Innocent se so, olùsò àgùntàn rè pastor David Ibiyeomie ni won fún ní okò bògìnì tí ó wà ní ìsàlè yí gégé bi èbùn ojó ìbí rè, sé kò dùn gbó l’étí ni?. Ó ye kí ...

Read More »
Saakashvili

The Crooks, the Clowns and the Nazis – a dynamic analysis

This article was written for the Unz Review The latest big news out of the Ukraine Have you heard what the latest big news out of the Ukraine is? No? There is a mini-Maidan under way and Ukrainian nationalists seem to ...

Read More »
kurds

Game over: How the Kurds lost the high risk gamble

By Aram Mirzaei As predicted, the Kurdish referendum ended in a conflict over the disputed areas in northern Iraq, areas that have been occupied by Kurdish Peshmerga forces since the 2014 ISIL invasion of Iraq. Throughout these weeks, Kurdish media close ...

Read More »
syria

Syria War Report – October 25, 2017: US-backed Forces Seize More Oil Fields In Deir Ezzor Province

Late on October 24, the US-backed Syrian Democratic Forces (SDF) accused the Syrian Arab Army (SAA) of attacking its units on the eastern ban of the Euphrates, near Deir Ezzor city. The incident allegedly took place at Jubaylah. According to ...

Read More »

Òrò ni *IFÁ*.

    Òpolopò ènìyàn ni kò mo ìyàtò láàrin *IFÁ àti OLÓDÙMARÈ*. Òrò ni ifá, èyí tí ó ti enu Olúdùmarè wá tí ó fi rán *ÒRÚNMÌLÀ*

Read More »

Mike Ozekhome se ayeye ojó-ìbí rè nígbà tí ó pé ogóta odún(60).

Gbajúgbajà amòfin oloyè Mike Ozekhome, SAN se ayeye ojó ìbí rè nígbà tí ó pé ogóta odún ni ilé-ìtura Sharaton tí ó wà ní ìlú Abuja nínú àwon tó lo ni Ààre télè Goodluck Jonathan, ìyàwó rè Patience, igbákejì Ààre ...

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb