Home / Art / Àṣà Oòduà / A kú àyájó odún *Òmìnira* ti *orílè Èdè Nàìjíríà* ?? lónìí ooo.
Nigeria Flag

A kú àyájó odún *Òmìnira* ti *orílè Èdè Nàìjíríà* ?? lónìí ooo.

A kú àyájó odún *Òmìnira* ti *orílè Èdè Nàìjíríà* ?? lónìí ooo. Èmí wa yóò se púpò rè láyé.
E jòwó, e má sì gbàgbé láti se *ìwúre* fún orílè èdè *Nàìjíríà* ?? nítorí wí pé *”Ìròrùn igi ni ìròrùn eye”*. Àgbájo owó la fi ñ sòyà, àjèjé owó kan kò gbérù dórí.

A sì tún kú àmójúbà *osù Òwàwà (October) tuntun*. Osù aláyò ni yóò jé fún wa láse Èdùmàrè. Èmi ò ní dòkú, èyin náà ò ní dòkú, gbogbo wa ni a yóò rí òpin odún yìí láyò àti àlááfíà… *(Ase! )*
????????
*omo oòduà rere ń kì I yín…

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...