Home / Art / Àṣà Oòduà / Adelabu tún gbé Ṣeyi Makinde lọ sí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn
Governor Seyi Makinde

Adelabu tún gbé Ṣeyi Makinde lọ sí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn

Adelabu tún gbé Ṣeyi Makinde lọ sí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn

Fẹ́mi Akínṣọlá

Àwọn àgbà ní bí o bá nídíì,arúgbó ò gbọdọ̀ sunkún ọmú.
Bayo Adelabu ti ẹgbẹ́ òsèlú APC ní òun kò faramọ́ ìdájọ́ Àjọ Elétò Ìdìbò tó ní Ṣeyi Makinde ló wọlé nínú ìdibò tó kọjá.


Oloye Adebayo Adelabu ti ẹgbẹ́ oselu APC ti ni, òun kò faramọ idajọ ajọ eleto idibo to da igbẹjọ oun nù lórí idibo to gbe Ṣeyi Makinde wọle gẹ́gẹ́ bi gomina nipinlẹ Ọyọ. Lẹ́yìn ọjọ mọkanlelogun ti idajọ naa waye ni ilu Ibadan, ni Adelabu gbe ẹjọ lọ ile ẹjọ kotẹmilọrun.


Adelabu ati ẹgbẹ oselu APC sọ wi pe, magomago waye ninu idibo Ọjọ Kẹsan, Osu Kẹta, ọdun 2019, eleyii to gbe Ṣeyi Makinde wọle gẹgẹ bi gomina.
Adelabu wa n beere lọwọ ile ẹjọ kotẹmilọrun lati sọ wi pe oun lo ni ibo to pọju lọ ninu idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ọyọ abi ki wọn tun ibo naa di.
Tí a ko ba gbagbe, Alaga igbẹjọ naa, Justice Muhammed Sirajo salaye pe awọn da ẹjọ ti APC pe mọ Ṣeyi Makinde nu nitori gbogbo àwọn ẹlẹri ti Adelabu pèé kò ní ẹri tó daju, amọ ti wọ́n ń sọ ahesọ lásán.

Iroyinowuro

About Lolade

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Olugbo

Oodua History 101: Meet the King that never sold out Oodua race

Alaafin Oyo was initially regarded as the Paramount ruler in Oodua (Yoruba) Land because, Oyo happened to be an empire and political headquarter of some Oodua people (Yorubas). but it is trite to know that, Oyo Empire didn’t cover the entire Oodua (Yoruba) land but kings who are subservient or surbodinate to Alaafin or King whose land had been taken by conquest. Moreover, during colonial era some monarchs were elevated as a result of selling their subject into slavery to ...