Home / Art / Àṣà Oòduà / Olódùmarè mà tóbi lóba ooo.

Olódùmarè mà tóbi lóba ooo.

Olódùmarè mà tóbi lóba ooo.

Kíni olórun olódúmarè kò le se tán, Olódùmarè tó dá ayé òhun òrun tí ó sì so òrò sí órìlè ayé, òrò náà á máa jé Ifá tí ó fi rán òrúnmìlà baba àgbónìrègún.
Òdú ìfá ni ó sì n se atóka ohun gbogbo, odù ifá náà bèrè láti orí Èjìogbè dé Òfún méjì.
Olódùmarè ti se atóka rè sí orílè alàyè a sì rí odù Ejìogbè ní ara Eranko Ewúró.
Njé Olódùmarè yí kò tóbi bí.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...