Home / Art / Àṣà Oòduà / *ORIN ORILE EDE NAIJIRIA NI EDE YORÙBÁ*
Nigeria Flag

*ORIN ORILE EDE NAIJIRIA NI EDE YORÙBÁ*

  1. ESE KINNI_
    Dìde Èyin Ará
    Waká jé ipe Nàijíríà
    K’à fife sin ‘lè wá
    Pel’ókun àt’sígbàgbó
    Kìse Àwon Àkoni wá,
    kò máse já s’ásán
    K’à sin t’òkan tará
    Ilé t’ómìnira,àt’àláfíà
    So d’òkan.

*ESE KEJI*
Olórun Elédàá
Tó ipa Ònà wa
F’ònà hàn asáajú
K’ódòó wa m’òtító
K’ódodo àt’ìfé pòsi
K’áyé won jé pípé
So wón d’eni gíga
K’álàfíà òhun ètó lè
Joba ní’lè wa.

*IJEJE*
Mo sè Ìlérí fún Orílè-Èdè mi Nàijíríà,
Láti jé olódodo, enití Ó see f’okàn tàn-án
Àti olótìtóó ènìyàn
Láti sìn ín pèlú gbogbo agbára mi,
Láti sa ipá mi gbogbo fún ìsòkan rè
Àti láti gbé e ga fún Iyì àt’Ògo rè.
Kí Olórun ràn mí l’ówó.

About Awoyemi Bamimore

One comment

  1. Orin na dun gidi gan. Mo feran re pupo

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...