Home / News From Nigeria / Breaking News (page 125)

Breaking News

Arákùnrin tí ó n se yahoo ni ó ti ya wèrè nígbá tí bàbá eè kú tán ní ìlú Benin.

Kàyéfì nlá ni ó jé nígbà tí Arákùnrin kan ya wèrè ní ìlú Benin ní ìpínlè Edo. Gégé bí ìròyìn se so, òdókùnrin yí ni won fi èsùn kàn wípé isé kí á máa fi èro gbáni ni ó n ...

Read More »

Mr Harri se ìgbéyawó pèlú ohun èlò orin tí a mò sí guitar ní ìpínlè Eko.

Arákùnrin kan ní orílè èdè Nìjíríà ti ya òpò èyan lénu látàrí sése ìgbéyàwó pèlú ohun èlò orin tí a mò sí guitar rè. Tí e bá rò wípé e ti ri tán , eléyìí tún ya ni lénu ò. ...

Read More »

Olùsò àgùntàn tí a mò sí pásítò Adeboye tí ó jé olórí àwon omo léyìn Jésù ti ìjo RCCG fún àwon akékòó ìmò adajó tí ó yege jùlo mérin ní Fìlà orí ri awon adájó àti aso won.

Olórí àwon olùfokànsìn àti omo léyì jésù ti Ìjo àwon RCCG, gbogbo àgbáyé, Pásítò E.A Adeboye fún àwon akékòó tí won sèsè gboyè gégé bíi adájó mérin nínú ìjo rè ní àgbàlá HALL OF MERCY, Bwari ní ìpínlè Abuja, ní ...

Read More »

Àwon àwòrán tí ó rewà tí Lota Chukwu fi se ayeye ojó ìbí rè nígbá tí ó pé omo odún mókàndínlógbòn (29).

Àwon àwòrán tí ó rewà tí Lota Chukwu fi se ayeye ojó ìbí rè nígbá tí ó pé omo odún mókàndínlógbòn (29). Gbajúgbajà arewà òsèré orílè èdè Nìjíríà tí ó n jé Lota Chukwu se ayeye odún mókàndínlógbon ojó ìbí ...

Read More »

Arábìnrin omo odún méèdógbòn, tí ó tún jé a fi ewà s’oge, Chidimma Leilani Aaron ti gba àmì èye gégé bíi omidan àkókó ní orílè èdè Nìjíríà tí odún 2018.

,Chidimma Leilani Aaron, omo odún méèdógbòn láti ìpínlè Enugu ti tayo àwon métàdínlógún (17) tí won jo díje fún omidan àkókó ní orílè èdè Nìjíríà ti odún yí. O di eni kejìlélógójì tí yóò gba àmì èye yí ó sì ...

Read More »

Tobi Bakre ya àwòrán pèlú Rita Dominic, Lolu, Bovi àti Ebuka.

Ará ilé BBNaija télè tí ó sì jé àyànfé òpò ènìyàn tí a mò sí Tobi Bakre lo sì orí èro ayélujára rè tí ó n jé Insítágírámù láti pín àwòrán òhun àti àwon ènîyàn pàtàkì bíi Rita Dominic, Lolu, ...

Read More »
truth

Truth!

Òsá Òtúrá says, “What is Truth?” I say, “What is Truth?” Ọ̀rúnmìlá says, “Truth is the Lord of Heaven guiding the Earth.” Ọ̀rúnmìlá says, “Truth is the Unseen One guiding the Earth. The wisdom of Olódùmarè he is using.” Òsá ...

Read More »

Following the Reaper Gleaners of Eji Koko Iwori

Eni a ba wa’de Laa ba rele Eni aja bawa laja nba lo Dia fun Eleji Iwori Ti yoo teju no akapo re girigiri Ebo ni won ni o wase O gbebo, o rubo Ifa teju mo mi koo wo ...

Read More »

Marriage: London Police Tell Yoruba Mother Home Truth (Video)

Officers from the Metropolitan Police in London have taken time out to minister to Yoruba women in the UK on why they should protect the sanctity of marriage. Led by a Yoruba speaking officer, the police were seen in a ...

Read More »
Ajaokuta Steel Plant

Woman of Steel : Senatorial candidate pledges to bring back Ajaokuta, NIOMCO

Candidate of the Social Democratic Party (SDP) for Kogi Central District in the 2019 election, Natasha Akpoti says if elected, she’d push for the resuscitation of the moribund multi million dollars Ajaokuta Steel Complex and the National Iron Mining Ore ...

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb