Home / News From Nigeria (page 184)

News From Nigeria

Seyi Makinde

Seyi Makinde di gómìnà kẹ́ta tó kó àrùn Covid-19

Oni ogbon ojo, osu keta ni ayewo gomina ipinle Oyo, Alagba Seyi Makinde jade, ti ayewo naa si gbee pe o ni arun naa. Oun ni o maa je eleeketa gomina ni orileede yii ti ayewo fihan pe won ni ...

Read More »
buhari

FG Assisted Fund: Every BVN Holder Should Be Expecting Their ₦30,000 Before the Next 24hours

In the recent statement released by the ministry of finance,the content of the statement affirmed and assured Nigerians who have been expecting the proposed #30,000 by the federal government as a result of the on going lockdown in some parts ...

Read More »
fg

Orí kó ènìyàn márùn-ún yọ lọ́wọ́ coronavirus l’Ekoo

Orí kó ènìyàn márùn-ún yọ lọ́wọ́ coronavirus l’EkooÌròyìn láti ọwọ́ Yínká Àlàbí Alaisan marun-un ninu awon ti arun buruku covid-19 ti n ba finra lati bii ose meloo kan seyin gba idande. Yoruba bo “won ni alaare ko ki n ...

Read More »
coronavirus

Ènìyàn tó ní àrùn coronavirus wọ 131 ní Naijiria

Ènìyàn tó ní àrùn coronavirus wọ 131 ní NaijiriaÌròyìn láti ọwọ́ Yínká Àlàbí Eniyan ogun lo tun kun awon ti arun coronavirus n ba ja ni orileede yii ni oni ogbon ojo, osu keta odun 2020.Metala ni Eko, merin ni ...

Read More »
seyi makinde

Ṣèyí Mákindé, gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìpàdé ètò ọrọ̀ aje Nàìjíríà l’òun ti kó àrùn COVID-19

Ṣèyí Mákindé, gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìpàdé ètò ọrọ̀ aje Nàìjíríà l’òun ti kó àrùn COVID-19

Read More »
Switzerland

SITREP: What the Covid-19 Pandemic Has Already Changed in Switzerland – and what not

There is a lot of speculation about the future of the planet, after the present crisis. This is a natural reaction.

Read More »

Crisis As Doctors, Nurses Pick Race After Suspected Coronavirus Cases Hit Lagos Hospital

The patients were brought in a private vehicle around midnight, with one of them coughing uncontrollably and showing other symptoms of coronavirus.

Read More »
Ìtànkálẹ̀ Àrùn Coronavirus Nílẹ̀ Amerika Ti Ju Ti Italy Àti China Lọ!

Ìtànkálẹ̀ Àrùn Coronavirus Nílẹ̀ Amerika Ti Ju Ti Italy Àti China Lọ!

Ìlẹ̀ Amẹ́ríkà mà ti gba ipò kínní gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè tí ìtànkálẹ̀ Coronavirus ti pọ̀jù lọ l’ágbàáyé pẹ̀lú ènìyàn tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà márùndínláádọ́rún tó ti ní àrùn náà.

Read More »
coronavirus

Ojúmọ́ Kan, Oògùn Kan

Ilu nla bii orileede Naijiria sowon lagbaye. Ko si odun kan tabi osu kan to le lo lofee ki o ma se si ohun kan ti a maa gbe poori enu. Igba miiran, o le je Obasanjo lo maa ko ...

Read More »
Nipa rogbodiyan ajakale arun coronavirus to n ja kaakiri agbaye to si tun ti rapala wo orileede Naijiria lati bii ose merin seyin. Ijoba ipinle Eko ti ti awon oja ti kii se ti ounje jijie ati mimu. Awon eniyan si n yo ijoba ipinle Eko lenu pe ki o ti gbogbo ilu pa lo le segun arun naa daadaa. Sanwo-Olu da won lohun pe arun naa ko ti ran de iye to le mu ki ijoba ti gbogbo Eko nitori ipo ti ipinle naa wa ni orileede yii. Gomina Sanwo-Olu tun salaye awon to maa letoo si ounje ofe. O ni awon ti eya ara pe nija ati awon arugbo ni eto naa koko wa fun bayii. O ni bi agbara ba se n de sii ni o maa so bi awon se maa te siwaju nipa iranlowo naa. Bayii eniyan aadorin (70) lo ti ko arun buruku naa ti merinlelogoji (44) si sele ni ipinle Eko. Ki Eledua ba wa segun ajakale arun naa.

Sanwo-olu Máa Fún Ẹgbẹ̀rún Lọ́nà Igba Ènìyàn Lóúnjẹ L’eko

Nipa rogbodiyan ajakale arun coronavirus to n ja kaakiri agbaye to si tun ti rapala wo orileede Naijiria lati bii ose merin seyin. Ijoba ipinle Eko ti ti awon oja ti kii se ti ounje jijie ati mimu. Awon eniyan ...

Read More »

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb