Home / News From Nigeria (page 342)

News From Nigeria

E wo aso Ebuka níbi ìgbéyàwó alárédè ti Banky W àti ìyàwó rè, Adesua Etomi.

Òpò ni ara ti n yá tí won sì ti fi ojú s’ónà láti wo aso tí Ebuka ma wò ní òtè yí báwo ni ó ti è se ma rí nínú rè ni ìbéèrè àwon ènìyàn, bí ó tilè ...

Read More »

Àwòrán ìsìnkú Akékòó jáde ti ilé èkó gíga Nnamdi Azkiwe (UNIZIK) tí ó kú ní òsè mélòó séyìn.

Olóògbé Arábìnrin Amaka Ezeokoli tí ó kú ní òsè mélòó séyìn léyìn àìsàn péréte , se ni won ti sin-ín ní ojó Àbáméta (Saturday) ní ìlú tí won bi sí ní Ezioko ní ìjoba ìbílè Gúúsù ti Orumba tí ó ...

Read More »

Banky W àti Adesua Etomi fi enu ko ara won lénu níbi ayeye ìgbéyàwó alárédè won ní orílè èdè South Africa .

” O le wá fi enu ko ìyàwó lénu báyìí” ni ó ma n dùn jù nínú ìgbéyàwó, tí kò bá rí béè Banky W àti Adesua kò bá má se tó báyìí, won ti fi enu ko ara lénu ...

Read More »

Ìsìnkú àwon tí won kú níbi ìjàmbá okò tí ó selè láìpé ní ìpínlè Imo.

Gégé bí Holychidi Ojlkorie, ìgbákejì olùgba oko àti aya n’ímòràn ti ìjoba ní ìpínlè Imo télè, òpò ènìyàn bí ogbòn ni won kú níbi ìjàmbá burúkú tí ó selè láìpé láàrin glokò epo petiróòlù àti okò èrò elérò méjìdínlógún (18) ...

Read More »

Banky W àti Adesua Etomi ya àwòrán pèlú àwon òbí won níbi ìgbéyàwó alárédè won.

Banky W àti Adesua Etomi ya àwòrán pèlú àwon òbí won níbi ìgbéyàwó alárédè won. Tokotayà tuntun, Banky W àti Adesua Etomi pèlú ègbón Adesua Etomi okùnrin, ìyá rè àti àwon òbí oko ní apá òtún èyí ma tún dára ...

Read More »

Banky W àti òré tímótímó tí ó rè le lo gba ìyàwó rè ( Adesua Etomi), Tunde Demuren .

Banky W àti òré tímótímó tí ó rè le lo gba ìyàwó rè ( Adesua Etomi), Tunde Demuren . Banky W àti òré rè tímótímó fún ìgbéyàwó alárédè rè, Tunde Demuren ni won Jo ya àwòrán papò níbi ìgbéyàwó alárinrin ni ...

Read More »

Oritsefemi dòbálè ní iwájú àwon àna rè, àwon òbí Nabila Fash níbi ayeye ìgbéyàwó ìbílè won.

Oritsefemi àti àwon òré rè ti dòbálè níwájú àwon ebí ìyàwó rè tí a mò sí àna rè níbi ìgbéyàwó náà, ìgbéyàwó náà dára púpò. N se ni ó dàbí kí èmi náà lo se ìgbéyàwó báyìí.

Read More »

Òòsà Roman lo sí ibi ayeye ìgbéyàwó alárédè ti Oritsefemi àti ìyàwó rè, Nabila Fash, níbi tí ó ti wo aso tí àyà rè hàn.

   Gbajúgbajà tí olórun fún ní èbùn tí ó bùáyà, tí a mò sí òòsà obìnrin ti ilè Roman lo sí ibi ayeye ìgbéyàwó alárédè ti Oritsefemi àti Nabila Fash pèlú àyà rìwòwò tí olórun fún lo sí ibi ayeye ...

Read More »

Oritsefemi ná owó fún ìyàwó rè , Nabila Fash níbi ìgbéyàwó ìbílè rè.

Oritsefemi ná owó fún ìyàwó rè , Nabila Fash níbi ìgbéyàwó ìbílè rè. Oritsefemi àti ìyàwó rè, Nabila Fash ti se ìgbéyàwó ní ilú èkó, e tún wo àwòrán Àkàrà òyìnbó won (Cake) tí tokotayà sì n wo ojú ara ...

Read More »

Àwòrán Oritsefemi àti Nabila Fash léyìn tí won se ìgbéyàwó ìbílè ní òwúrò tán kí ó tó di wípé won se ti alárédè.

Àwòrán Oritsefemi àti Nabila Fash léyìn tí won se ìgbéyàwó ìbílè ní òwúrò tán kí ó tó di wípé won se ti alárédè. Oritsefemi àti ìyàwó rè tí tè síwájú fún ìgbéyàwó alárédè . E wo Nabila Fash bí ó ...

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb