Home / Art / Àṣà Oòduà / Omiyalé, àgbàrá ya sóòbù ní ìlú ilé-ifè.

Omiyalé, àgbàrá ya sóòbù ní ìlú ilé-ifè.

Ní òwúró ojó àíkú tí se èní,ojó kokàndínlógbòn osù keje odún 2018 ni òjò yí bèrè tí ó sì kò tí kò dáké di bíi agogo márùn-ún ìròlé.

Èyí fa kí àgbàrá ya wo ilé tí ó pò ní òpópónà Ede sí ifè, àti ònà tí a mò sí road 7, àti àwon ònà míràn, Ó tilè ti férè gba ilé míràn lówó onílé.

Tí ó bá je wípé ó ńkó wólo ni Ó sì dára, sùgbón kò wó lo bíkòse wípé ó dúró sí ojú kan tí kò sì lo, báwo ni àwon tí ó wà nínú ilé se ma jáde àti wípé báwo ni àwon tí ó wà ní ìta se ma w’olé?

Ìsèlè yí, nínú ìwádìí a gbó wípé èyí kó ni àkókò tí omi ma w’olé tí àgbàrá sì ma wo sóòbù ní ilé ifè ìlú tí ó wà ní ìpínlè Òsun ní orílè èdè Nìjíríà.
Kí ni ó le fa èyí? Sé ònà tí kò dára ni àbí àílè se ònà tí ó ye kí àgbàrá ma gba, èyí mà le poo, ní ìlú tí mùndùnmúdùn gbé ń sàn fún wàrà àti oyin, “èbè ni a be àwon ìjoba wa kí won bá wa mójú tó àwon ònà yí nítorí olórun” báyìí ni àwon ará ìlú ńké.

About Awoyemi Bamimore

One comment

  1. OLAMILEKAN

    Ko tiri, me man koru ye n’fe

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...