Home / News From Nigeria / World News / Ó dèèwo̩ f’ó̩kùnrin lati gun kè̩ké̩ e̩lé̩se̩ mè̩ta pè̩lú obìnrin – Gaduje
Ganduje

Ó dèèwo̩ f’ó̩kùnrin lati gun kè̩ké̩ e̩lé̩se̩ mè̩ta pè̩lú obìnrin – Gaduje

Ó dèèwo̩ f’ó̩kùnrin lati gun kè̩ké̩ e̩lé̩se̩ mè̩ta pè̩lú obìnrin – Gaduje

Gomina ipinle Kano, Alhaji Umar Gaduje lo soo dofin nibi idanilekoo awon Musulumi kan to waye ni ipinle naa.


O ni lati odun 2020 to n bo, okunrin kankan ko gbodo wo keke Marwa tabi Keke Napep pelu obinrin kankan ni ipinle Kano.

Gomina salaye siwaju sii pe , ipinle Musulumi ti awon eniyan fi n se awokose ni ilu Kano, awon ko si gbodo yinge ninu gbogbo nnkan daadaa ti aye mo awon si. O ni nipa idi eyi enikeni to ba ru ofin lati ojo kin-in-ni osu kin-in-in odun to n bo yoo rugi oyin.


Gaduje ni agbere bere lati ara fifi ara ko ara lati inu keke, ni eyi ti Olorun lodi si gidigidi.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...