Bí Kunle Ọlasọpe, ìlúmọ̀ọ́ká agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ṣe lo ìgbésí ayé rẹ̀ rèé o. Fẹ́mi Akínṣọlá Àwọn àgbà bọ wọ́n níjọ́ a kú,làá dère,èèyàn ò sunwọ̀n láàyè. ọrun dẹ̀dẹ̀ má kánjú gbogbo wa la ń bọ̀.Olóògbé Kunle Ọlasọpe, tíí ṣe ọkunrin akọkọ ...
Read More »
ayangalu Comments Off on O̩kùnrin àkó̩kó̩ lórí Te̩lifísò̩n l’Áfíríkà filè̩ bora
Bí Kunle Ọlasọpe, ìlúmọ̀ọ́ká agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ṣe lo ìgbésí ayé rẹ̀ rèé o. Fẹ́mi Akínṣọlá Àwọn àgbà bọ wọ́n níjọ́ a kú,làá dère,èèyàn ò sunwọ̀n láàyè. ọrun dẹ̀dẹ̀ má kánjú gbogbo wa la ń bọ̀.Olóògbé Kunle Ọlasọpe, tíí ṣe ọkunrin akọkọ ...
Read More »ayangalu Comments Off on Èèyàn tó pọ̀ ní Nàìjíríà kìí ṣe dúkìá, gbèsè ni – Sanusi
Èèyàn tó pọ̀ ní Nàìjíríà kìí ṣe dúkìá, gbèsè ni…Sanusi Fẹ́mi Akínṣọlá Emir ilu Kano, Mohammadu Lamido Sanusi (II) sọ oko ọrọ kan niluu Abuja lọjọ Aje nibi to ti sọ pe gbese ni iye eeyan to wa lorilẹ-ede Nàìjíríà ...
Read More »Lolade Comments Off on Adelabu tún gbé Ṣeyi Makinde lọ sí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn
Adelabu tún gbé Ṣeyi Makinde lọ sí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Fẹ́mi Akínṣọlá Àwọn àgbà ní bí o bá nídíì,arúgbó ò gbọdọ̀ sunkún ọmú.Bayo Adelabu ti ẹgbẹ́ òsèlú APC ní òun kò faramọ́ ìdájọ́ Àjọ Elétò Ìdìbò tó ní Ṣeyi Makinde ...
Read More »ayangalu Comments Off on Odu, “Ogunda tua”, cast for yesterday’s Ose Ifa
Looking at the Odu, “Ogunda tua”, cast for today’s Ose Ifa, I can boldly say that we are all “Aborisa”( worshippers of Orisa). Just Iisten:- Ìyere àràmùAdífá fún won nílùú ÀpekusinbaWon ò mo Òòsà tí won ó moo bo ni ...
Read More »ayangalu Comments Off on Alagba, The Oldest Tortoise In The World
The Oyinbos have agenda of totally erasing the Africa History and we are ignorantly assisting them. I read a report written by some conspiracy theorists on BBC (The father of Propadanda) this morning about the oldest tortoise, Alagba, who died ...
Read More »ayangalu Comments Off on Soworẹ́ Gbòmìnira Láhàmọ́ Ọ́ Dss Pẹ̀lú Ọgọ́rùn Ún Mílíọ̀nù Náírà
Soworẹ́ gbòmìnira láhàmọ́ ọ́ DSS pẹ̀lú ọgọ́rùn ún mílíọ̀nù náírà Fẹ́mi Akínṣọlá Èèyàn téégún ń lé,kó máa rọ́jú,bó ṣe ń rẹ ará ayé,náà ló ń rèrò ọ̀run. Àgbálọ gbábọ̀, ilé ẹjọ́ gíga t’ìjọba àpapọ̀ l’Abuja ti gba béèlì Omoyele Soworẹ́ ...
Read More »Ilééṣẹ́ Aṣọ́bodè Naijiria ń pa bílíọ̀nù N5.8 wọlé lójúmọ́ Fẹ́mi Akínṣọlá Ṣe n ta o ba fẹ ba fẹ o bajẹ, o ní ba a ṣe e ṣe e.N lo bi ọrọ kan ti ọ̀ga agba asọbode ilẹ yìí sọ ...
Read More »ayangalu Comments Off on Ìjàpá Tó Wà Ní Ààfin Ṣọ̀ún Ògbómọ̀ṣọ́ (Alàgbà) Ti Papòdà
Ìṣe èèyàn ,ìṣe ẹranko, Ìjàpá tó wà ní ààfin Ṣọ̀ún Ògbómọ̀ṣọ́ Alàgbà ti papòdà lẹ́ni ojilelọọdunrun ọdún ó lé mẹrin lóke eèpẹ̀ . Fẹ́mi Akínṣọlá Toyin Ajamu, to jẹ akọwe agba ni Ààfin Kabiyesi Ṣọun ti ilẹ Ogbomọṣọ ti bùn ...
Read More »ayangalu Comments Off on Artist: Moyo Okediji
My motherWho walks in the nightGraceful be thy stepsAs you place your heelOn the head Of a hidden Cobra And it cannot bite you.
Read More »ayangalu Comments Off on 615″, ńọ́ń́bà tuntun fún ìdáàbòbò àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀
“615”, ńọ́ń́bà tuntun fún ìdáàbòbò àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Fẹ́mi Akínṣọlá Awọn agba bọ wọn ni oju bayii ni alakan fii sọri.Eyi naa lo mu gomina ipinlẹ Oyo,Ṣeyi Makinde gbe igbesẹ akin, ni bi o ṣe kede ńọ́ń́bà Ẹẹfa, ookan, ...
Read More »
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more